Numbers 12:6-8

6Ó wí pé, “Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi:

“Bí wòlíì Olúwa bá wà láàrín yín
Èmi Olúwa a máa fi ara à mi hàn án ní ojúran,
Èmi a máa bá a sọ̀rọ̀ nínú àlá.
7 aṢùgbọ́n èyí kò rí bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú Mose ìránṣẹ́ mi:
ó jẹ́ olóòtítọ́ nínú gbogbo ilé mi.
8 bMo sì ń bá a sọ̀rọ̀ ní ojúkojú,
ọ̀rọ̀ yékéyéké tí kì í ṣe òwe,
ó rí àwòrán Olúwa
Kí ló wá dé tí ẹ̀yin kò ṣe bẹ̀rù
láti sọ̀rọ̀-òdì sí Mose ìránṣẹ́ mi?”
Copyright information for YorBMYO